Tuesday, April 15, 2014
IBUKUN YANTURU - Opolopo ni ona ti ibikun
Monday, April 14, 2014
Yoruba religion - South-West Nigeria springs
When we talk about Yoruba or Yoruba religion, the African race particularly the Yoruba people of South-West Nigeria springs to mind. Nope! There are Yoruba aboriginals in Togo and Benin Republic.
There are native Caribbeans and South Americans who have adopted Yoruba culture and most interestingly, they passionately follow our own ancestral faith “The Yoruba Religion” called Santeria (Lucumi) in the Americas.
Photo: Babalawo Fabunmi performing the Ifa divination on some Ifa devotees.
Sunday, April 13, 2014
Oriki Ibeji (Twins)
This Panegyric Is Dedicated To Our 'Twins' Members
Ejire oyila winiwini loju orogun, ejiworo loju iya re
Mba bejire mbayo, O be kisi be kese, ofese me jejeji be sile alakisa
O so alakisa di onigba aso, okan ni mba bi mba yo, sugbon meji lo wole tomiwa,
Gbajumo omo ti ngba ikunle iya, ti ngba idobale lowo baba to bi won lomo
Ejire ara isokun, edunjobi omo edun tin sere ori igi
Taani eni naa to so wipe kosi olorun?
Abamo Ni Gbeyin Oro Abamo
~Femi Ojewale
ITAN: Ni ilu ti mo de
Ni ilu ti mo de yi ni won ti je k'oyemi pe pipa ni won maa n pa awon Agunbaniro ti o ba fun awon Omobinrin won loyun. N ko se meni se meji, mo gbe apo irinajo mi, o di'lu Abuja lodo Roselini, arabinrin ti o ba mi se'to bi won se gbemi lo si ilu Kantaga yii, ibi ti awon Obinrin rin won ki i ti ba awon Agunbaniro lo.
Ero meji ni o wa si mi lokan: Akoko ni pe n ko so pe n o k'enu Ife si awon Omobinrin ibe o, sugbon ise temi gege bi Oluko nibe, n je ko ni si igba ti emi ati awon omo wonyi yoo ma sere bi kaf'orow'oro ni? Abi ki Oluware kan dake kale bi Olundu ni won fe? Ekeji ni pe awon Omobinrin ti o wa nilu yii rewa ju ki n ma bawon sere oge lo. Won pon dele bi olele awe. Oju won gun rege. Ikebe won ju Olumo rooki lo. Irun ori won n bena yan-yan-yan bi igba ti ara ba san loju orun.
Saturday, April 12, 2014
BOKO HARAM KIN LO DE.
Subscribe to:
Posts (Atom)